Yọ̀mí Fash-Láńsò (tí wọ́n bí ní Ọjọ́ keje oṣù kẹfà ọdún 1968) jẹ́ gbajúmọ̀ òṣèré ọmọ bíbí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.[1] [2]
Yọ̀mí Fash-Láńsò kàwé gboyè dìgírì nínú
Yọ̀mí Fash-Láńsò | |
---|---|
Ọjọ́ìbí | Ọjọ́ keje oṣù kẹfà ọdún 1968 |
Ọmọ orílẹ̀-èdè | Nàìjíríà |
Iléẹ̀kọ́ gíga | University of Lagos. |
Iṣẹ́ | òṣèré |
Notable work | Aje metta |
imọ̀ nípa okowò ní ifáfitì ìjọba àpapọ̀ tí ó wà ní ìpínlẹ̀ Èkó, University of Lagos. Gẹ́gẹ́ bí a ti mọ̀ pé Yọ̀mí di gbajúmọ̀ òṣèré ìlúmọ̀ọ́kà ní sinimá àgbéléwò èdè Yorùbá, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ní àmìn ẹ̀yẹ tí ó ti gbà.[3] [4]
|url-status=
ignored (help)